IRỌ́ LÓRÍ IRỌ́
Ní kété tí Èdùmàrè bá ti ṣe àfihàn lílé àwọn ìjọba agbésùnmọ̀mí nàìjíríà kúrò lórí ilẹ̀ wa, tí Ìjọba-Adelé wa ti wọlé sí’nú gbogbo oríkò ilé-iṣẹ́ Ìjọba káàkiri ìpínlẹ̀ méjèèje, ní Democratic Republic of the Yoruba (D.R.Y), tí ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ iṣẹ́ bẹ̀rẹ̀ tààrà, lọ́gán ni àṣírí máa tú nípa oríṣiríṣi irọ́ tí òyìnbó-amúnisìn tí Ọlọ́run ti […]