ÒGO ỌLỌ́RUN NÍNÚ ỌMỌ YORÙBÁ
Nínú gbogbo ọ̀rọ̀ tí Ìránṣẹ́ Olódùmarè, Màmá wa, Ìyá-Ààfin Modúpẹ́ Onítirí-Abíọ́lá, máa nbá wa sọ, gbólóhùn kan sábà máa nwáyé: èyíinì ni “Ògo Ọlọ́run.” Wọ́n sábà máa nsọ fún wa pé, “Ní dédé àsìkò yí, ní dédé ìgbà yí, Ọlọ́run fẹ́ kí a pàdà sí Orísun wa, kí á kúrò ní oko ẹrú, kí á […]