Kíni A Npè Ní Ay’edèrú Onjẹ?
Ẹ jẹ́ kí a ṣọ́’ra fún irúfẹ́ onjẹ tí a njẹ, ní àkókò yí. Nígbàtí a bá ti lé àwọn agbésùnmọ̀mí ìj’ọba Nàìjíríà kúrò l’orí ilẹ̀ wa tán, ìj’ọba Orílẹ̀-Èdè Olómìnira Tiwantiwa ti Yorùbá máa ri dá’jú wípé gbogbo ohun tí a máa máa jẹ s’ẹnu ní ilẹ̀ Yorùbá máa jẹ́ inkan tí kò l’ewu […]