Ó Màṣe Ò! Ọ̀dọ́’mọkùnrin Kan Ṣe’kúpa Bàbá Rẹ̀ Láti Fi Ṣe Ètùtù Ọlà!
Fọ́nrán kan tí ó tẹ̀ wá lọ́wọ́ ni a ti rí ọ̀dọ́’mọdékùnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ridwan Adewale tí ó sì ń kà bòòròbò, arákùnrin yí ṣe ikú pá bàbá rẹ̀, ó ní òhún fi ṣe ètùtù ọlà nítorí àìríjẹ. Ọ̀dọ́’mọdékùnrin náà ṣeé láàyè wípé, nígbà tí ìyà náà pọ̀ lápọ̀jù ni òhun […]