Ọ̀NÀ MÍRÀN TÍ ÀWỌN ALÁWỌ̀ FUNFUN TÚN FẸ̀ GBÀ LÁTI PA ÀWA ÁFRÍKÀ RUN
Nínú ìròyìn kan tí ó tẹ̀ wá lọ́wọ́ ni a ti gbọ́ nípa ìpàdé tí àwọn ìgbìmọ̀ tí ó ń rí sí ìṣẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì nípa ìlera ènìyàn tí àwọn Àjọ fún Ètò Ìlera Àgbáyé (WHO) ṣe láìpẹ́ yí, kókó ohun tí ìpàdé wọn dá lé lórí ni, àrùn kan tí wọ́n ń pe orúkọ rẹ̀ ní […]