Oríṣiríṣi Ọ̀rọ̀ Tí Kò Ní Ìtumọ̀ Láti Ẹnu Àjọ Ecowas!
A kì í ní k’ọ́mọ ẹni má d’ẹ́tẹ̀, tó bá ti lè dá’gbó gbé ECOWAS tún ti gbé tuntun dé o! Àwọn wo ni ECOWAS? Àwọn apapọ̀ orílẹ̀-èdè ní ìwọ̀-oòrùn Áfríkà, tí wọ́n pa ara wọn pọ̀ láti dòwò papọ̀ látàrí kí ọ̀rọ̀ ajé ó lè dẹrùn káàkiri agbègbè náà. Ṣùgbọ́n ṣá o, láti iye […]