Òyìnbó Njowú Ìṣẹ̀dá Aláwọ̀dúdú
Oríṣiríṣi nkan ni a ti gbọ́ nípa bí àwọn òyìnbó amúnisìn ṣe fẹ́ kó aláwọ̀dúdú kúrò nílẹ̀, kí wọ́n lè gba ilẹ̀ wa, èyí tí ó jẹ́ ilẹ̀ ọlọ́ra; àti kí àlùmọ́nì ilẹ̀ wa ó lè di tiwọn pátápátá láìsí àtakò kankan. Ṣùgbọ́n, kìí wá nṣe èyí nìkan ni àwọn òyínbó wọ̀nyí nwá o! Paríparì […]