ÒṢÌṢẸ́ PA Ọ̀GÁ WỌN NÍ ÌLÚ ÀKÚRẸ.. HÀÀ!
Àwọn òṣìṣẹ́ méjì kan, àwakọ̀ àti olùrànlọ́wọ́-iṣẹ́, ni a gbọ́ pé wọ́n kó àwọn míràn mọ́ra, tí ó jẹ́ pé wọ́n wá ṣekú pa ọ̀gá wọn, Abilékọ Ọlákúnbi Adene, tí ó jẹ́ gbajúmọ̀ olónjẹ ní ìlú Àkúrẹ́, ní Orílẹ̀-Èdè Olómìnira Tiwantiwa ti Yorùbá wa yí. Ọ̀rọ̀ gbogbo lórí alábahun ni ọ̀rọ̀ yí jẹ́ o – […]