Ọ̀RỌ̀ ÒMÙGỌ̀ LẸ́NU ỌMỌ ÍBÒ
Ó pẹ́ tí a ti máa ń sọ pé àwọn ọmọ Íbò gọ̀, wọ́n nf’ẹnu họ’ra. Ṣé láìpẹ́ yí ni ìkan nínú wọn tún bọ́ sórí ẹ̀rọ ayélujára tó sì ń wí pé, àwọn Yorùbá ń bẹ̀rù láti kúrò nínú Nàìjíríà. Ẹ jọ̀wọ́ ẹ bá wa béèrè lọ́wọ́ alákọrí rẹ̀ bóyá ihò-ilẹ̀ ló ń gbé, […]