• Oríkò Ilé-Iṣẹ́ Ìjọba, Agodi, Ìpínlè Ìbàdàn (Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ látijọ), D.R.Y
The youngest nation in the world is the democratic republic of the Yoruba. The 55th nation in Africa

Àwa Ojúlówó Ọmọ Òmìnira Yorùbá Àtàtà Kìí Ṣe Ajìjàgbara Mọ́ Ooo

A Ríkà Nínú Ìwé Ìròyìn Pilot Ti Ọjọ́ Jimo, Ọjọ́ Kẹrìnlá Oṣù Kẹfà Ọdún Ẹgbàá-Ó-Lé-Mẹ́rin-Lé-Lógún Wípé Àwọn Kan Tí Wón Pé Ara Wọn Ní Yorùbá Nation Agitators Gba’ná Jẹ Fún Àwọn Tí  Wọ́n Pe Ara Wọn Ní Gómìnà Ìwọ-Oorun Nigeria Wípé Dandan Ni Kí Àwọn Gba Òmìnira Fún Yorùbá, He Èé!, Yorùbá Èwo Tún Ní?, […]

Read more
The youngest nation in the world is the democratic republic of the Yoruba. The 55th nation in Africa

Ilẹ̀ Yorùbá, Agbára Ọ̀dọ́

Awọn bàbá wa sọ wípé, Ọmọdé gbọ́n, Àgbà gbọ́n, laafi dá’lẹ̀ Ifẹ̀. Bẹ́ẹ̀ náà ni wọ́n sọ wípé, Ọwọ́ ọmọdé kò tó Pẹpẹ; ṣùgbọ́n, àgbàlagbà tí ọwọ́ rẹ̀ tó pẹpẹ nkọ́? ti ó bá gbé kèrègbè l’ati orí pẹpẹ, à ti mú nkan t’ó wà nínú kèrègbè náà nkọ́? Ọwọ́ àgbàlagbà ti tóbi jù l’ati […]

Read more
The youngest nation in the world is the democratic republic of the Yoruba. The 55th nation in Africa

Àwọn Orúkọ Ní’lẹ̀ Yorùbá Tí Ó Ngbé Àwọn Akọni L’arugẹ Tàbí Àṣà Yorùbá

A tún ntẹ̀ síwájú, l’oní, nípa sís’ọ̀rọ̀ nípa àwọn orúkọ ìlẹ̀ Yorùbá. Yàtọ̀ sí orúkọ àmút’ọ̀runwá, a lè sọ ọmọ wa ní oríṣiríṣi orúkọ tí ó bá wù wá. Orúkọ tí a bá fún ọmọ wa, yàtọ̀ sí orúkọ àmút’ọ̀runwá; òun ni a mpè ní ORÚKỌ ÀBÍSỌ. Kì nṣe gbogbo ọmọ ni ó ní orúkọ […]

Read more
The youngest nation in the world is the democratic republic of the Yoruba. The 55th nation in Africa

Mẹ́wàá Nṣẹlẹ̀ Nílẹ̀ Yorùba!

Hmmm, nǹkan ń kán, mẹ́wàá ń ṣẹlẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá! Àjálù iná tó jó ilé ní Erékùṣù Èkó ní ọdún k’ọ̀la ṣe wá ní kàyéfì. Ṣùgbọ́n àwọn bàbá wa bọ̀, wọ́n wí pé “Bí nǹkan kò ba ṣe ẹ̀sẹ́, ẹ̀sẹ́ kìí déédéé sẹ́. Ṣé Olójú kò ní r’ójú e ni’le, kó sọ pé kó fọ́, àjókòó-dìde […]

Read more
The youngest nation in the world is the democratic republic of the Yoruba. The 55th nation in Africa

Ajá T’ó Fẹ́ Sọnù Ni Nàìjíríà!

Bẹ́ẹ̀ ni, ọ̀rọ̀ ajá t’ó fẹ́ sọnù ni ọ̀rọ̀ Nàìjíríà, kò níí gbọ́ fèrè ọdẹ! Òwe Ìkìlọ̀ Yorùbá A tún ti gbọ́ ìròyìn míràn tí ó fi hàn gbangba wípé Nàìjíríà ṣì pàpà nka ilẹ̀ Yorùbá mọ́ ìlú Nàìjíríà, l’ẹhìn ìgbà tí Orílẹ̀-Èdè Olómìnira Tiwantiwa ti Yorùbá ti di orílẹ̀-èdè aṣe’jọba-ara-ẹni! Èyí ni ó jẹ […]

Read more
The youngest nation in the world is the democratic republic of the Yoruba. The 55th nation in Africa

Ìjọba Agbésùnmọ̀mí Nka Yorùbá Mọ́ Naìjíría! Hábà!

Ìjọba Nàìjíríà, tí ó jẹ́ ìjọba agbésùnmọ̀mí tí wọ́n ndúkòkòlajà mọ́ ọmọ ìbílẹ̀ Yorùbá, lórí ilẹ̀ Babanlá wa, kòì tíì kúrò l’orí kí wọn máa purọ́ wípé Yorùbá ṣì wà l’ara Nàìjíríà. Èyí tí wọ́n tún gbé dé ní àìpẹ́ yí ni wípé, wọ́n nka Èkó mọ́ àwọn ibi tí irin-iṣẹ́ tí ó nṣàkóso ètò […]

Read more
The youngest nation in the world is the democratic republic of the Yoruba. The 55th nation in Africa

Orúkọ Àmútọ̀runwá Nílẹ̀ Yorùbá

Yorùbá bọ̀, wọ́n ní “Orúkọ ọmọ ni ìjá’nu ọmọ.”  Òwe Yorùbá Oríṣiríṣi orúkọ l’ó wà ní ilẹ̀ Yorùbá. Àwọn Yorùbá kìí dédé fún ọmọ l’orúkọ láì ní ìdí pàtàkì. Ìdí ni’yí tí wọ́n fi np’òwe wípé “Ilé l’a nwò, kí á tó s’ọmọ l’orúkọ.” Orúkọ Àmútọ̀runwá Èyí jẹ́ àwọn orúkọ tí a nsọ àwọn ọmọ […]

Read more
The youngest nation in the world is the democratic republic of the Yoruba. The 55th nation in Africa

Ọmọ Ìbílẹ̀ Yorùbá

Sé ní àípẹ́ yi ni a sọ ìdí pàtàkì tí ó fi jẹ́ wípé a kò le gbé irúfẹ́ ìgbé ayé tí ó yẹ k’á gbé gan-gan, láì jẹ́ wípé a gbé ìgbé-ayé wa ní ìbámu pẹ̀lú ìṣẹ̀dá wa, tí èyí sì bẹ̀rẹ̀ pẹ̀lú ìṣẹ̀dá Yorùbá, ní’wọ̀n ìgbà tí ó ti jẹ́ wípé ìṣẹ̀dá Yorùbá […]

Read more
The youngest nation in the world is the democratic republic of the Yoruba. The 55th nation in Africa

Kò Sí Òfò Tàbí Àdánù Ninú Ìṣèlú Àti Ìṣe’jọba Orílẹ̀-Èdè Yorùbá

Ọ̀pọ̀l’ọpọ̀ ìgbà ni a ti gbọ́ l’ati ẹnu Ìránṣẹ́ Olódùmarè, Màmá Modúpẹ́ Onítirí-Abíọ́lá, wípé orílẹ̀-èdè Yorùbá jẹ́ èyí tí kò ní sí òfò tàbí àdánù kankan ní ètò ìṣè’jọba rẹ̀. Ẹ má ṣe jẹ́ kí èyí kí ó ṣe wá ní kàyéfì rárárárá o! Ara àgbékalẹ̀ fún ìgbáyégbá’dùn ọmọ ìbílẹ̀ Yorùbá nìyẹn. A níl’ati mọ̀ […]

Read more
The youngest nation in the world is the democratic republic of the Yoruba. The 55th nation in Africa

Ìba’nújẹ́ L’apá Kan, Ìroyìn Ayọ̀ L’apá Kan!

Ohun t’ó dé, l’ó fa mo kó, mo rò! Òwe Yorùbá Agbésùnmọ̀mí Nigeria l’orí ilẹ̀ Orílẹ̀-Èdè Yorùbá, ṣebí òun l’ó fa gbogbo àrí’fín àti ìwọ̀sí Nigeria tí ó nta bá wa, l’oní. Ṣùgbọ́n, ní àìpẹ́ àti ní àìjìnà, ọmọ ìbílẹ̀ Yorùbá ti sọ wípé, gbogbo nkan burúkú tí a nrí l’orí ilẹ̀ wa báyi, a […]

Read more