Ó Gbẹnu Tán: Ẹ Wá Wo Bí Wọ́n Ṣe Ń Kó Gbogbo Agbára Sí Ọdọ Ara Wọn Ní Orílè-Èdè Nàìjíríà
Báwo ni ẹ ṣe fẹ́ kí ìdájọ́ òdodo wà ní orílè-èdè Nàìjíríà, ìjọba mọ́ mí kí ń mọ̀ ọ́ ni wọ́n ń fi ìjọba Nàìjíríà ṣe, a rí àṣírí èyí nínú ìj’ọ́mọ ènìyàn Justice Kayode Olú Ariwoọlá, kété ti wọn ti búra fún un tán gẹ́gẹ́ bíi adájọ́ àgbà ní orílè-èdè Naijiria ní ọjọ́ kẹta […]