• Oríkò Ilé-Iṣẹ́ Ìjọba, Agodi, Ìpínlè Ìbàdàn (Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ látijọ), D.R.Y
Democratic Republic of the Yoruba is known in history as Yoruba Kingdom, Yorùbá Nation, Yorubaland, and Yorùbá Country.

ÀBÁMỌ̀ NÍÍ GBẸ̀YÌN Ọ̀RÀN

Ẹ̀rọ ayélujára X, ló gbé fọ́nrán ọkùnrin àgbé’nipá’wó kan jáde níbi tí wọ́n ti ń fi ọ̀rọ̀ wá a lẹ́nu wò, tí ó sì wá ń tọrọ àforíjì báyìí wípé kí wọ́n sáànú òun, ó ní òun kábáámọ̀ ìgbésẹ̀ náà,àti pé ìgbà àkọ́kọ́ ni eléyìí. Ọ̀ jálé onílé fi bo tirẹ̀ lẹ́yìn, ó wípé, owó […]

Read more
Democratic Republic of the Yoruba is known in history as Yoruba Kingdom, Yorùbá Nation, Yorubaland, and Yorùbá Country.

ÌTÀNJẸ LÁSÁN NI ABẸ́RẸ́ COVID 19

Ọkùnrin òyìnbó kan fi àìdùnnú rẹ̀ hàn nípa abẹ́rẹ́ àjẹsára covid 19, ó wí pé, ìdí tí àwọn ìjọba wọn fi mú àwọn ènìyàn ni dandan láti gba abẹ́rẹ́ ọ̀hún kò yé òun rárá nítorí pé kò sí iṣẹ́ kankan tí ó ṣe láti dènà àìsàn náà. Ó tẹ̀síwájú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, gẹ́gẹ́ bí […]

Read more
Democratic Republic of the Yoruba is known in history as Yoruba Kingdom, Yorùbá Nation, Yorubaland, and Yorùbá Country.

EWÉ ÀTI EGBÒ

Láti ìgbà ìwásẹ̀ ni Olódùmarè ti fún àwọn babańlá  wa ní ọgbọ́n, ìmọ̀ àti òye, láti lè bá ewé sọ̀rọ̀, àti oríṣiríṣi ohun tí ó wà ní àyíká wa; bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ní ìmọ̀ àwọn ohun tí èwé, egbò, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ le ṣe, pàápàá ní àgọ́-ara. Èyí ló ṣe okùnfà oríṣiríṣi ìwòsàn tí àwọn […]

Read more
The youngest nation in the world is the democratic republic of the Yoruba. The 55th nation in Africa

ÒTÍTỌ NÍPA ÌWÀ KÍKÓNI L’Ẹ́RÚ

Obìnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Candace Owens, sọ̀rọ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára nígbàtí ó ń ṣàlàyé nípa ọ̀rọ òwò ẹrú ní Áfríkà. Ó ní àwọn ènìyàn sọ pé ìkónilẹ́rú ní Áfríkà bẹ̀rẹ̀ láti ọwọ́ àwọn aláwọ̀ funfun Yúróòpù. Ó wípé kò rí bẹ́ẹ̀ ràrá o. Gẹ́gẹ́bí ó ṣe sọ; ó ní ó pọ̀ ní […]

Read more
Democratic Republic of the Yoruba is known in history as Yoruba Kingdom, Yorùbá Nation, Yorubaland, and Yorùbá Country.

ỌMỌ ADÉBÓYÈ JÍ BÍLÍỌ̀NÙ MẸ́JỌ NÁÍRÀ

Ọmọ àlùfáà Adébóyè, tí orúkọ rẹ̀ njẹ́ Adéolú Adébóyè, ni ìròhìn tẹ̀ wá lọ́wọ́ ní yàjóyàjó pé ó jí bílíọ̀nù mẹ́jọ owó náírà ní Nàìjíríà, látàrí pé ó ti gba owó yí sápò, fún iṣẹ́ pópónà ní Ìpínlẹ̀ Kaduna wọn lọ́hun, gẹ́gẹ́bí agbaṣẹ́ṣe. Lẹ́hìn tí ó ti gba òbítíbitì owó yí, ìròhìn náà sọ pé […]

Read more
Democratic Republic of the Yoruba is known in history as Yoruba Kingdom, Yorùbá Nation, Yorubaland, and Yorùbá Country.

OJÚ OLÈ RÈÉ! ÀÀRẸ ÀWỌN GBÉWIRI! 

Èèyàn bí ìgbín ní hè gbín, ẹni bí ahun níí r’áhun he, Láìpẹ́ yìí ní fọ́nrán kan tó ti fi ìgbà kan jà rànhìn-rànhìn lórí ẹ̀rọ ayélujára tún padà jáde o, níbi tí a ti rí ọkàn lára àwọn olóṣèlú ìlú agbésùnmọ̀mí Nàìjíríà tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Umar Ganduje tó ti ń gba owó […]

Read more
Democratic Republic of the Yoruba is known in history as Yoruba Kingdom, Yorùbá Nation, Yorubaland, and Yorùbá Country.

IGI Ọ̀PẸ OLÓRÍ PÚPỌ̀ NÍ ILẸ̀ YORÙBÁ 

Tí a bá ń sọ̀rọ̀ nípa ìran tí Olódùmarè dá ní àrà ọ̀tọ̀, ipò Kínní ni ìran Yorùbá wà, látàrí àwọn ohun àrà tí Olódùmarè dá s’órí ilẹ̀ Yorùbá. Láìpẹ́ yìí ní a gbọ́ nípa igi ọ̀pẹ kan tí ó ní orí márùndínláàádọ́ta,tí a bá wo igi náà láti ìsàlẹ̀, ọ̀kan ṣoṣo ni, ṣùgbọ́n ní’pele-ní’pele […]

Read more
Democratic Republic of the Yoruba is known in history as Yoruba Kingdom, Yorùbá Nation, Yorubaland, and Yorùbá Country.

ILÉ-Ẹ̀KỌ́ Ọ̀FẸ́

A dúpẹ́ lọ́wọ́ Adániwáyé tó sọ ohun gbogbo di ọ̀tun fún wa Ní orílẹ̀ èdè Olómìnira Tiwantiwa ti Yorùbá (Democratic Republic of the Yorùbá D.R.Y), tí a bá wo orílẹ̀ èdè agbésùnmọ̀mí Nàìjíríà tí a ti kúrò, a ó ríi bí ètò ẹ̀kọ́ wọn ṣe mẹ́hẹ, púpọ̀ ọmọ tó yẹ kó wà ní ilé-ẹ̀kọ́ ló […]

Read more
Democratic Republic of the Yoruba is known in history as Yoruba Kingdom, Yorùbá Nation, Yorubaland, and Yorùbá Country.

ÈÈMỌ̀ WỌ̀’LÚ!! OBÌNRIN TÓ Ń TA ORÍ ÈNÌYÀN

“Ẹ jọ̀wọ́, ẹ ṣàánú fún mi, mi ò ní ṣe bẹ́ẹ̀ mọ́, mi ò kìí se apànìyàn, ọrọ̀ ajé ní mo ṣe dé ‘bẹ̀.” Báyìí ni obìnrin kan ṣe ń sọ pẹ̀lú omijé lójú nínú fọ́nrán tí wọ́n ti nfi obìnrin náà han pé ó ń ta orí ènìyàn. Obìnrin náà ṣe àlàyé pé ọkùnrin […]

Read more
Democratic Republic of the Yoruba is known in history as Yoruba Kingdom, Yorùbá Nation, Yorubaland, and Yorùbá Country.

NÀÌJÍRÍÀ, JÁWỌ́ KÚRÒ LÁRA D.R.Y

Orílẹ̀-Èdè Olómìnira Tiwantiwa ti Yorùbá (Democratic Republic of the Yoruba, D.R.Y) ti jáde kúrò lára Nàìjíríà láti ogúnjọ́ oṣù bélú, ẹgbàá-ọdún ó lé méjì-lé-lógún, bẹ́ẹ̀ ni a ti bẹ̀rẹ̀ ìṣèjọba-ara-ẹni tiwa láti ọjọ́ kéjìlá oṣù igbe, ẹgbàá ọdún ó-lé-mẹ́rinlélógún, èyí tí ó túmọ̀ sí pé ọ̀ràn-dídá gbáà ni fún Nàìjíríà láti máa ṣe ohunkóhun lórí ilẹ̀ […]

Read more