ÀWỌN ỌMỌ ÍBÒ TÚN TI BẸ̀RẸ̀ SÍÍ KỌJÁ ÀYÈ WỌN: WỌ́N MÁA TẸ́ !
Ìròhìn tí ó tẹ̀ wá lọ́wọ́ fi hàn pé, ẹ̀tẹ́ àwọn ọmọ Íbò lórí ilẹ̀ Yorùbá, kù sí dẹ̀dẹ̀. A kúkú ti mọ̀ wọ́n tẹ́lẹ̀ sí alágídí; bẹ́ẹ̀ ni wọ́n máa nsọ̀rọ̀ láì fi làákàyè si: ṣé wọ́n rò pé Orílẹ̀-Èdè Olómìnira Tiwantiwa ti Yorùbá jẹ́ Nigeria ni? Dájú-dájú, ọ̀rọ̀ ti kàn wọ́n lára pé […]