ÒKÚ Ọ̀RỌ̀ TÍ WỌ́N FI Ń DUN ÀWỌN ÌGBÒ NÍNÚ
Òkú ọ̀rọ̀ tí ìròyìn kan gbé jáde ní orí ẹ̀rọ ayélujára , nípa ọkùnrin Yorùbá kan tí wọ́n ní ó bẹ̀rẹ̀ sí ní mú orí àwọn ìran Ìgbò wú lòdì, nígbà tí ó ṣe àlàyé ọ̀rọ̀ kan wípé, àwọn Ìgbò ni wọ́n kó ipa tí ó pọ̀ jùlọ nínú ìdàgbàsókè ọrọ̀ ajé gbogbo àgbáyé. Ọkùnrin […]