PÀṢÍPÀRỌ̀ ỌMỌ ỌWỌ́
Ó ti dójú ẹ̀ báyìí. Ó sì gba omijé lójú ẹni tó bá mọ iyì ọmọ. Yorùbá bọ, wón ní, ọmọ ni iyì, ọmọ lèrè, ọmọ laṣọ, ọmọ lalẹ́. Ṣùgbọ́n nínú fọ́nrán kan tí a rí lórí ayélujára, ọmọ ọwọ́ oṣù márùn-ún ti wá di ohun tí a nfi ṣe pàṣípààrọ̀ fún ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ ti […]
AJÍNIWÒ!
Ìlú agbésùnmọ̀mí nàìjíríà, tí ó ń fipá jẹ gàba lórí ilẹ̀ wa, Democratic Republic of the Yoruba láìní ẹ̀tọ́ kankan lábẹ́ òfin ní àgbáyé láti ṣe bẹ́ẹ̀, tí ó sì jẹ́ ìwà ọ̀daràn, ìwà ìkọlu-orílẹ̀-èdè-míràn èyí tí ó jẹ́ orílẹ̀-èdè aṣejọba-ara-ẹni ti ara rẹ̀. Ìlú agbésùnmọ̀mí Nàìjírìà jẹ́ ìlú tí ó ń jí ohun tí wọ́n […]
ÀǸFÀÀNÍ ORÍLẸ̀-ÈDÈ OLÓMÌNIRA TIWANTIWA TÍ YORÙBÁ: ÈTÒ ÌRÌNNÀ OJÚ PÓPÓ
Ní Orílẹ̀ èdè Olómìnira Tiwantiwa ti Yorùbá (Democratic Republic of the Yorùbá D.R.Y), ohun gbogbo ni ètò ti wà fún, láti ọjọ́ Kejìlá oṣù Igbe ẹgbàáọdúnólémẹ́rìnlélógún tí a ti ṣe ìbúra wọlé fún olórí adelé wá bàbá wa Mobọlaji Ọlawale Akinọla Ọmọkọrẹ ni àwọn adelé wa sì ti ń mú’sẹ́ ṣe láti ríi dájú pé […]
ÌKỌJÁ ÀÀYÈ GIDI
Ìròyìn kan gbé Ipinnu ìjọba agbésùnmọ̀mí Nàìjíríà jádè nípa ìgbésẹ wọn láti kọ́ ẹnu ibodè sí àwọn òpópónà márosẹ̀ ni ìlú wọn láti lè ma gba owó ọ̀nà lọ́wọ́ àwọn tó nwakọ̀ kọjá níbẹ̀. Bi kò bá ṣe pé wọ́n darukọ àwọn ìlú tó jẹ́ tí Orílẹ̀ Èdè Olómìnira Tiwantiwa ti Yorùbá (Democratic Republic of […]
ÌLÚ AGBÉSÙNMỌ̀MÍ NÀÌJÍRÍÀ PẸ̀LÚ ÌWÀ IBI RẸ̀
Olódùmarè má jẹ̀ẹ́ kí ayé wa dàbí ìlú aríremáṣe nàìjíríà, ìlú tí wọ́n ń fi ìwà ibi yangàn tí wọ́n sì ń gbilẹ̀ nínú rẹ̀, oníkálukú ló ń ṣe òfin lọ́wọ́ ara rẹ̀, òfin kò sí fún olówó, tálíkà nìkan ni ó wà fún, èyí wá fún kálukú láàyè láti ma pa èlòmíràn l’ẹ́kún jayé. […]
ÀǸFÀÀNÍ ORÍLẸ̀-ÈDÈ OLÓMÌNIRA TIWANTIWA TÍ YORÙBÁ: KÒ NÍ SÍ ÀYÈ FÚN RÌBÁ
Àlàkalẹ̀ ètò ìsèjọba orílẹ̀ èdè Olómìnira Tiwantiwa ti Yorùbá (Democratic Republic of the Yorùbá D.R.Y) tí Olódùmarè fún màmá wá, ìyá ààfin Modupẹọla Onitiri-Abiọla, kò fi àyè sílẹ̀ fún rìbá tàbí owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ rárá, yálà ní ilé iṣẹ́, ní ilé ìwé, nínú ètò òṣèlú àti ní oríṣiríṣi ẹ̀ka. Ẹnikẹ́ni tó bá gbìyànjú láti ṣe lòdì […]
AMÚNISÌN ŃṢE’KÚPA ÀWỌN OLÓRÍ
Ìgbàkúgbà tí olórí kan bá ti ń ṣe dáradára fún àwọn orílẹ̀-èdè rẹ̀ ní Áfríkà, ṣe ni àwọn òyìnbó amúnisìn máa ń ṣekúpa irúfẹ́ olórí bẹ́ẹ̀, tàbí kí wọ́n ba ìlú jẹ́ mọ́ọ lọ́wọ́. Ọkùnrin aláwọ̀dúdú kan ni ó sọ ọ̀rọ̀ yí, ní orí ẹ̀rọ Ayélujára TikTok, ìkànnì @africaonepeace. Ó wá dárúkọ̀ lára àwọn tí […]
ÀWỌN ÌYÀWÓ ILÉ TI DI OLÓṢÓ TÁN
Nínú fọ́nrán kán lórí ayélujára ni a ti ri ọkùnrin báálé ilé kan, tó fi ìkorò-ọkàn kígbe pé owó tí wọn ngbà l’oṣù kò tó láti ra àpò irẹ̀sì kan. Kí ló fà á tí gbogbo nkan fi rí báyìí, nípasẹ̀ bí ọ̀rọ̀ yí ṣe ta bà wá ní Democratic Republic of the Yoruba (D.R.Y) […]
APANIMÁYỌDÀ ỌMỌ ÍBÒ
Ọkùnrin Ìgbò kan tí orúkọ rẹ̀ njẹ́ Emeka Madu, pẹ̀lú àwọn ọmọ Ìgbò ẹgbẹ́ rẹ̀ mẹ́rin, ní ìlú Ìkọ̀tún ní Ìpínlẹ̀ Èkó, Orílẹ̀-Èdè Olómìnira Tiwantiwa ti Yorùbá (Democratic Republic of the Yoruba, D.R.Y) wa yí, ni a rí fọ́nrán bí ó ṣe nṣe àwọn oògùn nínú ilé àlàpà, tí òògùn náà sì l’ewu. Ìyẹn tilẹ̀ […]
ORÍLẸ̀ ÈDÈ D.R.Y KÒ NÍ SÍ LÁBẸ́ ORÍLẸ̀ ÈDÈ KANKAN
Láìsí àní-àní, orílẹ̀ èdè Olómìnira Tiwantiwa ti Yorùbá (Democratic Republic of the Yorùbá D.R.Y) ti dúró, Olódùmarè ti fún wa ní òmìnira nípasẹ̀ màmá wa ìyá ààfin Modupẹọla Onitiri-Abiọla láti ogúnjọ́ oṣù Bélú ẹgbàáọdúnóléméjìlélógún bẹ́ẹ̀ni a ti ṣe ìbúra wọlé fún olórí adelé wá bàbá wa Mobọlaji Ọlawale Akinọla Ọmọkọrẹ ní ọjọ́ Kejìlá oṣù Igbe […]